ALAWIYE Blog

ALAWIYE Blog A ki yin kaabo s'ori a'pere ti o n gbaruku ti idagbasoke Asa ati Ise ede Yoruba. Alawiyeblog !!!
(1)

15/04/2026

Ọ̀rọ̀ rè é ooooo

Ǹjẹ́ ẹ̀yin rò pé ááwọ ló ń bẹ láàrin Gómìnà Seyi Makinde àti Olúbàdàn àbí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Òsèlú APC ló ń wọ́nà láti sọ Góminà Seyi Makinde lẹ́nu?

15/04/2026

Ǹjẹ́ ẹ̀yin mọ̀ pé alágbẹ̀dẹ kìí fi ohùn tàbí ẹnu dáhùn tí wọ́n bá kí i lẹ́nu isẹ́?

Ìkíni lẹ́nu isẹ́ Yorùbá.
Ẹ farabalẹ̀ gbọ́ bí alágbẹ̀dẹ se ń dáhùn lópin fọnran yìí.

15/04/2026

Ǹjẹ́ ẹ̀yin ròpé Oriyọmi Hamzat le mú ìlérí rẹ̀ sẹ fún Seyi Makinde mọ́?

15/04/2026

Fọ́nrán: Olóyè nínú ẹgbẹ́ òsèlú APC tẹ́lẹ̀rí -John Oyegun pariwo "APC" ní ìpàgọ́ gbogbogbo àwọn ADC

Credit: NJENJE media tv

Òtítọ́ nipé wọ́n ní kí ń gbìmọ̀ pọ̀ yọ Gómìnà Seyi Makinde kúrò lóyè sùgbọ́n mo kọ owó tí wọn fún mi- Debọ Ogundoyi, abẹ...
14/04/2026

Òtítọ́ nipé wọ́n ní kí ń gbìmọ̀ pọ̀ yọ Gómìnà Seyi Makinde kúrò lóyè sùgbọ́n mo kọ owó tí wọn fún mi- Debọ Ogundoyi, abẹnugan ilé igbìmọ̀ asofin ìpínlẹ̀ ìbàdàn

Fayose, Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ipínlẹ̀ Ekiti bẹ Olúbàdàn wo lórí ọ̀rọ̀ tí ó fi léde pé Gómìnà Sèyí Mákindé ń gbèrò láti yọ Olúb...
14/04/2026

Fayose, Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ipínlẹ̀ Ekiti bẹ Olúbàdàn wo lórí ọ̀rọ̀ tí ó fi léde pé Gómìnà Sèyí Mákindé ń gbèrò láti yọ Olúbàdàn lóyé.

Nkò ní agbára láti yọ Gómìnà nípò- Olubadan ké gbàjarè. Bákan náà, Olori Florence Ajimọbi náà ti fi àtẹ̀jáde síta pé irọ...
14/04/2026

Nkò ní agbára láti yọ Gómìnà nípò- Olubadan ké gbàjarè. Bákan náà, Olori Florence Ajimọbi náà ti fi àtẹ̀jáde síta pé irọ́ lásán ni àtẹ̀jáde tí Hon. Gbenga oyekọla fi síta.

Ẹ wo àtẹ̀jáde tí Hon. Gbenga Oyekọla fi síta nípa Olubadan àti Florence Ajimọbi tí wọ́n gbìmọ̀ láti yọ Makinde nípò?
14/04/2026

Ẹ wo àtẹ̀jáde tí Hon. Gbenga Oyekọla fi síta nípa Olubadan àti Florence Ajimọbi tí wọ́n gbìmọ̀ láti yọ Makinde nípò?

Gómìna ìpínlẹ̀ ògùn - Dapọ Abiọdun ti kéde Senator Solomon Olamilekan Adeola (Yayi) gẹ́gẹ́ bí ẹni tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òsèl...
14/04/2026

Gómìna ìpínlẹ̀ ògùn - Dapọ Abiọdun ti kéde Senator Solomon Olamilekan Adeola (Yayi) gẹ́gẹ́ bí ẹni tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú APC ipínlẹ̀ Ogun fẹnukò sí láti díje dupò Gómìnà lábẹ́ ẹgbẹ́ òsèlú wọn.

Ẹgbẹ́ òsèlú APC ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ńgbèrò láti yọ Gómínà Seyi Makinde kúrò lóyè- Hon. Gbenga Oyekọla sọ èyí lẹ́yin tí Olubada...
14/04/2026

Ẹgbẹ́ òsèlú APC ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ńgbèrò láti yọ Gómínà Seyi Makinde kúrò lóyè- Hon. Gbenga Oyekọla sọ èyí lẹ́yin tí Olubadan, ọba Rasheed Adewọlu Ladọja àti Ìyàwó Gómìnà àná, Florence Ajimọbi pe Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin ipínlẹ̀ Ọ̀yọ́- Debọ̀ Ogundoyin sí ìpàdé

Ǹjẹ́ ẹ̀yim mọ̀ọ́?
13/04/2026

Ǹjẹ́ ẹ̀yim mọ̀ọ́?

Olúbàdàn àti Gómìnà ipínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti sàlàyé pé kòsí òtítọ́ nínú ọ̀rọ̀ tí Gómínà tẹ́lẹ̀rí ti ìpílẹ̀ Ekiti- Fayose sọ nípa...
13/04/2026

Olúbàdàn àti Gómìnà ipínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti sàlàyé pé kòsí òtítọ́ nínú ọ̀rọ̀ tí Gómínà tẹ́lẹ̀rí ti ìpílẹ̀ Ekiti- Fayose sọ nípa pé Gómìnà Seyi Makinde ńgbèrò láti yọ Olúbàdàn nípò.

Address

Beere, Mapo
Ibadan

Alerts

Be the first to know and let us send you an email when ALAWIYE Blog posts news and promotions. Your email address will not be used for any other purpose, and you can unsubscribe at any time.

Share

Category