Yoruba Broadcasting Network YBN

Yoruba Broadcasting Network YBN HUB FOR TRENDING NEWS,INTERVIEWS,DOCUMENTARIES AND ENTERTAINMENT
(1)

27/08/2026

WON TI SE ALAYE IDI TI AWON OLOPA IPINLE KWARA SE FE WA GBE TANI OLOHUN NI IPINLE IBADAN

FULL NEWS: https://youtu.be/azdjD5AQqYI

27/08/2026

FROM YBN ARCHIVE

27/08/2026

*ÀKÓJỌPỌ̀ ÌRÒYÌN ÒWÚRỌ̀ ÒNÍ ỌJỌ́ KẸTÀDÍNLỌ́GBỌ̀N OṢÙ KẸ́JỌ ỌDÚN 2026*

1. *ÌJỌBA ÀPAPỌ̀ ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÌJÍRÍÀ TI JẸ́ KÓ DI MÍMỌ̀ PÉ BÍLÍỌ̀NÙ LỌ́NÀ ẸGBẸ̀TA NÁÍRÀ ( ) NI WỌ́N SAN FÚN ÀWỌN ẸBÍ TÓ TÓ MÍLÍỌ̀NÙ MẸ́WÀÁ TÓ KU DÍẸ̀ KÁÀ TÓ FÚN LÁÀRÍN ỌDÚN MẸ́TA*

2. *ÀJỌ ICRC TI ṢE ÀKỌSÍLẸ̀ Ẹ̀ PÉ ÀWỌN ẸGBẸ̀RÚN MẸ́TA ÈNÌYÀN (3,000) NI WỌ́N Ń WÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ NASARAWA LÉYÌÍ TÍ WỌ́N Ń WÁ ẸGBẸ̀RÚN MẸ́TÀDÍNLÓGÚN ÈNÌYÀN (17,000) NÍ ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÌJÍRÍÀ*

3. *ẸGBẸ́ ÒṢÈLÚ AFRICAN DEMOCRATIC CONGRESS (ADC) TI BÉÈRÈ FÚN NÍ NAWỌ́ GÁN ALÁGA KÁŃSÙ KÙJÉ ÌYẸN SAMUEL SHEKWOLO LÁTÀRI BÓ ṢE Ń DÚNKOKÒ PÉ KÍ ÀWỌN TÍ KÒ ṢE ÀTÌLẸ́YÌN FÚN ẸGBẸ́ ÒṢÈLÚ ALL PROGRESSIVES CONGRESS (APC) KÚRÒ NÍ OLÚ ÌLÚ WA ÀBÚJÁ*

4. *ÌJỌBA ÀPAPỌ̀ ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÌJÍRÍÀ TI BÉÈRÈ FÚN WÍWỌ́GI LÉ ÀDÉHÙN ÀTÚNṢE ÒPÓPÓNÀ BENIN SÍ ÀSÀBÀ*

5. *ILÉ IṢẸ́ ỌLỌ́PÀÁ ÌPÍNLẸ̀ Ọ̀YỌ́ TI NAWỌ́ GÁN ÀWỌN AFURASÍ MẸ́WÀÁ KAN TÍ WỌ́N Ń ṢE ÒWÒ KÁRÀKÁTÀ ẸRAN ỌMỌ ÈNÌYÀN*

6. *MALAMI TI YAN ÀWỌN ÈNÌYÀN TÍ WỌ́N TÓ ẸGBẸ̀TA (600) GẸ́GẸ́ BÍ ÌGBÌMỌ̀ IKỌ̀ OLÙPOLONGO ÌBÒ FÚN ẸGBẸ́ ÒṢÈLÚ AFRICAN DEMOCRATIC CONGRESS (ADC) NÍ ÌPÍNLẸ̀ KEBBI*

7. *ÀLHÁJÌ ABDULWAHEED AKÍNTỌ́LÁ ỌLÁJÍDÉ TÍ Ó TI FÌGBÀ KAN RÍ JẸ́ AKỌ̀WÉ FÚN ÌJỌBA ÌPÍNLẸ̀ Ọ̀YỌ́, TÍ Ó SÌ TÚN JẸ́ OLÓYÈ ŃLÁ NÍNÚ ẸGBẸ́ ÒṢÈLÚ ALL PROGRESSIVES CONGRESS (APC) TI DÁGBÉRE FÁYÉ*

8. *ONÍṢÈGÙN ÒYÌNBÓ KAN TÓ JẸ́ AKỌ́ṢẸ́MỌṢẸ́ NÍPA OJÚ TI JẸ́ KÓ DI MÍMỌ̀ PÉ ÀWỌN ỌMỌ ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÌJÍRÍÀ TÍ WỌ́N TÓ MÍLÍỌ̀NÙ MÉJÌ NI WỌ́N Ń GBÉ PẸ̀LÚ OJÚ FÍFỌ́ TÍ WỌ́N LÈ YẸRA FÚN*

9. *ORÍLẸ̀ ÈDÈ ISRAEL TI FÚN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÌJÍRÍÀ NÍ IPELE ÀKỌ́KỌ́ ÀWỌN ỌKỌ̀ PÀJÁWÌRÍ TÍ WỌ́N FI Ń KÓ ÀWỌN ALÁÌSÀN ÀTI ÀWỌN OUN ÈLÒ ÌMỌ̀ ÌṢÈGÙN*

10. *ALÁṢẸ BỌ́LÁ TINÚBÚ KẸ́DÙN IKÚ DỌ̀TUN ỌLÁDIPỌ̀ TÍ Ó JẸ́ AKỌ̀RÒYÌN ORÍ Ẹ̀RỌ AYÉLUJÁRA TI EAGLE*

11. *ÌJỌBA ÀPAPỌ̀ MÁA KÀN NÍPÁ FÚN ÀWỌN ILÉ Ẹ̀KỌ́ GÍGA, ILÉ ÌWÒSÀN ÌKỌNI LÁTI MÁA SAN OWÓ ORÍ ÀTI ÌDÍYELÉ INÁ MỌ̀NÀMỌ́NÁ*

12. *ÀTÍKÙ ÀBÚBÁKÀR ṢÌ TẸMPẸLẸ MỌ́Ọ PÉ ÒUN MÁA YỌ OWÓ ÌRÀNWỌ́ ORÍ EPO BÍ ÒUN BÁ GORÍ IPÒ ALÁṢẸ PẸ̀LÚ BÍ ÀWỌN ÈNÌYÀN ṢE Ń SỌ ÒGÚLÙTU Ọ̀RỌ̀ SÍI*

13. *ÌJỌBA ÌPÍNLẸ̀ Ọ̀ṢUN TI DÁ ÀWỌN ÀFỌBAJẸ LỌ́WỌ́ KỌ́ LÁTI FÒPIN SÍ GBOGBO ÈTÒ YÍYAN ỌBA ÌLÚ KÓKÀ MÌÍRÀN LÁSÌKÒ YÌÍ*

14. *ÀWỌN AJÍNIGBÉ TI JÍ AWAKỌ̀ ILÉ IṢẸ́ DANGOTE GBÉ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ÒGÙN BẸ́Ẹ̀ NI ÀWỌN ỌLỌ́PÀÁ TI BẸ̀RẸ̀ IṢẸ́ LÁTI ṢÀWARÍ Ẹ̀*

15. *ỌMỌ OGÚN ỌDÚN KAN (20YEARS) ṢÁ BÀBÁ Ẹ̀ LÁDÀ PA NÍ ÌPÍNLẸ̀ ANAMBRA*

*OLÚWATÓBILỌ́BA DÁRAMỌ́LÁ (GLAMOURLADY)*

*LÓ Ń JÁBỌ̀ ÌRÒYÌN ÒWÚRỌ̀ ÒNÍ FÚN ÌKÀNNÌ AMÓHÙNMÁWÒRÁN YORÙBÁ BROADCASTING NETWORK (YBN)*

Address

7 Akinolu Str, Victoria Island
Lagos
100001

Alerts

Be the first to know and let us send you an email when Yoruba Broadcasting Network YBN posts news and promotions. Your email address will not be used for any other purpose, and you can unsubscribe at any time.

Contact The Business

Send a message to Yoruba Broadcasting Network YBN:

Shortcuts

Share